Genesis 39:2-3
2
Olúwa
sì wà pẹ̀lú Josẹfu, ó sì bùkún un, ó sì ń gbé ní ilé ọ̀gá rẹ̀ ará Ejibiti.
3
Nígbà tí ọ̀gá rẹ̀ rí i pé
Olúwa
wà pẹ̀lú rẹ̀, àti pé
Olúwa
jẹ́ kí ó máa ṣe àṣeyọrí nínú ohun gbogbo tí ó dáwọ́ rẹ̀ lé.
Copyright information for
YorBMYO